Las preventas y novedades mas esperadas del año hasta 10% + envio gratis a partir de $50.000  Ver más

menú

0
  • argentina
  • chile
  • colombia
  • españa
  • méxico
  • perú
  • estados unidos
  • internacional
portada Ewì ÀṢeyẸ Òmìnira Nàíjíríà (en Africanos)
Formato
Libro Físico
Editorial
Idioma
Africanos
N° páginas
68
Encuadernación
Tapa Blanda
Dimensiones
22.9 x 15.2 x 0.4 cm
Peso
0.11 kg.
ISBN13
9786200620330

Ewì ÀṢeyẸ Òmìnira Nàíjíríà (en Africanos)

Funmilayo Adesanya-Davies (Autor) · Globeedit · Tapa Blanda

Ewì ÀṢeyẸ Òmìnira Nàíjíríà (en Africanos) - Adesanya-Davies, Funmilayo

Libro Nuevo

$ 75.833

$ 94.791

Ahorras: $ 18.958

20% descuento
  • Estado: Nuevo
Origen: Estados Unidos (Costos de importación incluídos en el precio)
Se enviará desde nuestra bodega entre el Lunes 05 de Agosto y el Lunes 19 de Agosto.
Lo recibirás en cualquier lugar de Argentina entre 1 y 3 días hábiles luego del envío.

Reseña del libro "Ewì ÀṢeyẸ Òmìnira Nàíjíríà (en Africanos)"

Èyí ni àwọn EWÌ ÀṢEYỌRÍ ÒMÌNIRA NÀÍJÍRÍÀ tí mo kó jọ papọ̀ Ó jẹ́ ohùn ìdùnnú fún mí púpọ̀ láti kọ ìwé àkójọpọ̀ ewì yìí. A kọ ìwé ewì yìí ni àsìkò tí orílẹ̀-èdè Nàíjíríà pé Ọgọ́ta Ọdún láti șe àyàjọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ náà; ti wón șe ÀṢEYỌRÍ ÒMÌNIRA ỌGỌTA ỌDÚN ORÍLẸ̀ ÈDÈ NÀÍJÍRÍÀ náà. Àwọn ewì jẹ ohun àbálàye tí ó jẹ ọmọ Yorùbá lógún. Ní ayé àtijọ́ ní ilè Yorùbá, ò un ni àwọn bàbá-ńlá wa máa ń lò fún ìmọ̀, ìmọ̀ràn àti ẹ̀kọ́, ṣùgbọ́n won kìí kọọ́ sílẹ̀ nítorí pé, wọn kò ní ìmọ̀ mọ̀ọ́kọ-mọ̀ọ́kà rárá. Orísírísí ewì ni ó wa, orísírísí ọ̀nà ni a sì lè pín ewì sí. Èrò ọkàn mí ní pé a ó gbàdùn ìwé àkójọpọ̀ ewì yìí. Nàìjíríà (/naɪˈdʒɪrɪə/) jẹ́ Orílẹ̀-èdè Olómìnira. Ìjọba Àpapọ̀ ilẹ̀ Nàìjíríà jẹ́ orílẹ̀-èdè tí ó ní ìjọba ìpínlẹ̀ mẹ́rindínlógójì tó fi mọ́ Agbẹ̀gbẹ̀ Olúìlú Ìjọba Àpapọ̀. Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà ní apá Iwọ̀ Oòrùn ilẹ̀ Áfríkà. Orílẹ̀-èdè yí pààlà pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Benin ní apá ìwọ̀ Oòrùn, ó tún pààlà pẹ́lú orílẹ̀-èdè olómìnira ti Nijẹr ní apá àríwá, Chad àti Kamẹróòn ní apá ìlà Oòrùn àti Òkun Atlantiki ni apá gúúsù. Abuja ni ó jẹ́ Olú-Ìlú fún orílẹ̀-èdè náà. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Nàìjíríà ní ẹ̀yà púpọ̀, àwọn ẹ̀yà mẹ́ta ni wọ́n tóbi jùlọ. Àwọn wọ̀nyí ni Ẹ̀yà Yorùbá, Ẹ̀ya Ìgbò ati Ẹ̀yà Hausa.

Opiniones del libro

Ver más opiniones de clientes
  • 0% (0)
  • 0% (0)
  • 0% (0)
  • 0% (0)
  • 0% (0)

Preguntas frecuentes sobre el libro

Todos los libros de nuestro catálogo son Originales.
El libro está escrito en Africanos .
La encuadernación de esta edición es Tapa Blanda.

Preguntas y respuestas sobre el libro

¿Tienes una pregunta sobre el libro? Inicia sesión para poder agregar tu propia pregunta.

Opiniones sobre Buscalibre

Ver más opiniones de clientes